a
Mt 22.32
;
Mk 12.26
;
Lk 20.37
;
Ap 3.13
;
7.32
.
Exodus 3:6
6
a
Nígbà náà ní ó wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu.” Nítorí ìdí èyí, Mose sì pa ojú rẹ̀ mọ́, nítorí ó bẹ̀rù láti bojú wo Ọlọ́run.
Copyright information for
YorBMYO